Àsọtẹ́lẹ̀ tí wòlíì Habakuku rí.
Copywork input for chapter 1 verse 1
Your input is saved to this browser automatically.
Olúwa, èmi yóò ti ké pẹ́ tó fún ìrànlọ́wọ́,
Copywork input for chapter 1 verse 2
Your input is saved to this browser automatically.
Èéṣe tí ìwọ fi mú mi rí àìṣedéédéé?
Copywork input for chapter 1 verse 3
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí náà, òfin di ohun àìkàsí,
Copywork input for chapter 1 verse 4
Your input is saved to this browser automatically.
“Ẹ wo inú àwọn kèfèrí, ki ẹ sí wòye,
Copywork input for chapter 1 verse 5
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí pé, èmi yóò gbé àwọn ara Babeli dìde,
Copywork input for chapter 1 verse 6
Your input is saved to this browser automatically.
Wọn jẹ́ ènìyàn ti a bẹ̀rù, tí a sì páyà,
Copywork input for chapter 1 verse 7
Your input is saved to this browser automatically.
Ẹṣin wọn yára ju ẹkùn lọ,
Copywork input for chapter 1 verse 8
Your input is saved to this browser automatically.
gbogbo wọn sì wà fún ìwà ipá
Copywork input for chapter 1 verse 9
Your input is saved to this browser automatically.
Wọn ó si máa fi àwọn ọba ṣẹ̀sín
Copywork input for chapter 1 verse 10
Your input is saved to this browser automatically.
Nígbà náà ni inú rẹ̀ yóò yípadà,
Copywork input for chapter 1 verse 11
Your input is saved to this browser automatically.
Olúwa, ǹjẹ́ láti ayérayé kọ ni ìwọ tí wà?
Copywork input for chapter 1 verse 12
Your input is saved to this browser automatically.
Ojú rẹ mọ́ tónítóní láti wo ibi;
Copywork input for chapter 1 verse 13
Your input is saved to this browser automatically.
Ìwọ sì tí sọ ènìyàn di bí ẹja inú Òkun,
Copywork input for chapter 1 verse 14
Your input is saved to this browser automatically.
Àwọn ènìyàn búburú fi àwọ̀n wọn gbé wọn sókè
Copywork input for chapter 1 verse 15
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí náà, ó rú ẹbọ sí àwọ̀n rẹ̀,
Copywork input for chapter 1 verse 16
Your input is saved to this browser automatically.
Ǹjẹ́ wọn yóò ha máa pa àwọ̀n wọn mọ́ ní òfìfo bí,
Copywork input for chapter 1 verse 17
Your input is saved to this browser automatically.