Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ nípa Ninefe. Ìwé ìran Nahumu ará Elkoṣi.
Copywork input for chapter 1 verse 1
Your input is saved to this browser automatically.
Ọlọ́run ń jẹ owú, ó sì ń gbẹ̀san,
Copywork input for chapter 1 verse 2
Your input is saved to this browser automatically.
Olúwa lọ́ra láti bínú, ó sì tóbi ní agbára;
Copywork input for chapter 1 verse 3
Your input is saved to this browser automatically.
Ó bá òkun wí, ó sì mú kí ó gbẹ;
Copywork input for chapter 1 verse 4
Your input is saved to this browser automatically.
Àwọn òkè ńlá wárìrì níwájú rẹ̀,
Copywork input for chapter 1 verse 5
Your input is saved to this browser automatically.
Ta ni ó lé dúró níwájú ìbínú rẹ̀?
Copywork input for chapter 1 verse 6
Your input is saved to this browser automatically.
Rere ni Olúwa,
Copywork input for chapter 1 verse 7
Your input is saved to this browser automatically.
ṣùgbọ́n pẹ̀lú ìkún omi ńlá
Copywork input for chapter 1 verse 8
Your input is saved to this browser automatically.
Kí ni ẹ̀yìn ń gbìmọ̀ lòdì sí Olúwa?
Copywork input for chapter 1 verse 9
Your input is saved to this browser automatically.
Wọn yóò sì lọ́lù papọ̀ bí ẹ̀gún òṣùṣú
Copywork input for chapter 1 verse 10
Your input is saved to this browser automatically.
Láti ọ̀dọ̀ rẹ, ìwọ Ninefe, ni ẹnìkan ti jáde wá
Copywork input for chapter 1 verse 11
Your input is saved to this browser automatically.
Báyìí ni Olúwa wí:
Copywork input for chapter 1 verse 12
Your input is saved to this browser automatically.
Nísinsin yìí ni èmi yóò já àjàgà wọn kúrò ní ọrùn rẹ
Copywork input for chapter 1 verse 13
Your input is saved to this browser automatically.
Olúwa ti fi àṣẹ kan lélẹ̀ nítorí tìrẹ Ninefe:
Copywork input for chapter 1 verse 14
Your input is saved to this browser automatically.
Wò ó, lórí àwọn òkè,
Copywork input for chapter 1 verse 15
Your input is saved to this browser automatically.