“Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yìn àlùfáà!
Àwọn ọlọ̀tẹ̀ ti gbilẹ̀ nínú ìpànìyàn
mo mọ ohun gbogbo nípa Efraimu
“Ìṣe wọn kò gbà wọ́n láààyè
Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí lé wọn;
Nígbà tí wọ́n bá lọ pẹ̀lú agbo ẹran
Wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Olúwa
“Fọn fèrè ní Gibeah,
Efraimu yóò di ahoro
Àwọn olórí Juda dàbí àwọn tí í
A ni Efraimu lára,
Mo dàbí kòkòrò aṣọ sí Efraimu,
“Nígbà ti Efraimu ri àìsàn rẹ̀,
Nítorí pé, èmi ó dàbí kìnnìún sí Efraimu,
Nígbà náà ni èmi ó padà lọ sí ààyè mi