“Sọ fún àwọn arákùnrin rẹ, ‘Ènìyàn mi,’ kí o sì wí fún àwọn arábìnrin rẹ ‘Àyànfẹ́ mi.’
Copywork input for chapter 2 verse 1
Your input is saved to this browser automatically.
“Ẹ bá ìyá yín wí, ẹ bá a wí,
Copywork input for chapter 2 verse 2
Your input is saved to this browser automatically.
Àìṣe bẹ́ẹ̀ èmi yóò tú u sí ìhòhò,
Copywork input for chapter 2 verse 3
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi kò ní fi àánú mi hàn sí àwọn ọmọ rẹ̀
Copywork input for chapter 2 verse 4
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí ìyá wọn ti hùwà àgbèrè,
Copywork input for chapter 2 verse 5
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí náà, èmi ó fi ẹ̀gún dì í lọ́nà,
Copywork input for chapter 2 verse 6
Your input is saved to this browser automatically.
Yóò sáré lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ ṣùgbọ́n kò ní bá wọn;
Copywork input for chapter 2 verse 7
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí pé kò tí ì mọ̀ pé èmi ni
Copywork input for chapter 2 verse 8
Your input is saved to this browser automatically.
“Nítorí náà, èmi yóò mú ọkà mi kúrò nígbà tó bá pọ́n,
Copywork input for chapter 2 verse 9
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi yóò sì fi ìwà ìtìjú rẹ̀ hàn
Copywork input for chapter 2 verse 10
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi yóò mú gbogbo ayọ̀ rẹ̀ wá sí òpin:
Copywork input for chapter 2 verse 11
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi yóò pa àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀ run,
Copywork input for chapter 2 verse 12
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi yóò bẹ̀ ọjọ́ Baalimu wò ní ara rẹ̀
Copywork input for chapter 2 verse 13
Your input is saved to this browser automatically.
“Nítorí náà, èmi yóò tàn án,
Copywork input for chapter 2 verse 14
Your input is saved to this browser automatically.
Níbẹ̀ ni èmi yóò ti dá ọgbà àjàrà rẹ̀ padà fún un,
Copywork input for chapter 2 verse 15
Your input is saved to this browser automatically.
“Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà,
Copywork input for chapter 2 verse 16
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi yóò mú orúkọ, àwọn òrìṣà Baali kúrò lẹ́nu rẹ̀;
Copywork input for chapter 2 verse 17
Your input is saved to this browser automatically.
Ní ọjọ́ náà, èmi yóò ṣe májẹ̀mú
Copywork input for chapter 2 verse 18
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi yóò fẹ́ ọ fún ara mi títí láé;
Copywork input for chapter 2 verse 19
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi yóò fẹ́ ọ fún ara mi ní òtítọ́
Copywork input for chapter 2 verse 20
Your input is saved to this browser automatically.
“Èmi yóò sì dáhùn ní ọjọ́ náà,”
Copywork input for chapter 2 verse 21
Your input is saved to this browser automatically.
ilẹ̀ náà yóò sì dá ọkà,
Copywork input for chapter 2 verse 22
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi ó sì gbìn ín fún ara mi lórí ilẹ̀ náà,
Copywork input for chapter 2 verse 23
Your input is saved to this browser automatically.