Efraimu ń jẹ afẹ́fẹ́;
Olúwa ní ẹjọ́ kan tí yóò bá Juda rò,
Láti inú oyún ni ó ti di arákùnrin rẹ̀ mú ni gìgísẹ̀,
Ó bá angẹli ja ìjàkadì, ó sì borí rẹ̀,
àní Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun;
Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀;
Oníṣòwò ń lo òsùwọ̀n èké
Efraimu gbéraga,
“Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ;
Mo sọ fún àwọn wòlíì,
Gileadi ha burú bí?
Jakọbu sálọ si orílẹ̀-èdè Aramu;
Olúwa lo wòlíì kan láti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti,
Ṣùgbọ́n Efraimu ti mú un bínú gidigidi;