Nígbà ti Efraimu bá ń sọ̀rọ̀, àwọn ènìyàn máa ń wárìrì,
JA
Copywork
Yoruba OYCB Hosea 13장
写経は速く終える入力練習ではなく、一節ずつみ言葉の文と流れを改めて受け止める時間です。入力内容はこのブラウザに一時保存され、ログインするとアカウントにも保存されます。
小見出し単位で進める · Hosea
Báyìí, wọ́n ń dá ẹ̀ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀;
Nítorí náà wọn yóò dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀,
“Ṣùgbọ́n Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ̀,
Mo ṣe ìtọ́jú rẹ ní aginjù,
Wọn ni ìtẹ́lọ́rùn nígbà tí mo fún wọn ní oúnjẹ,
Nítorí náà, Èmi yóò dìde sí wọn bí i kìnnìún,
Beari igbó tí a já ọmọ rẹ̀ gbà,
“A ti pa ọ́ run, ìwọ Israẹli,
Níbo ni ọba rẹ gbé wà nísinsin yìí kí ó bá à le gbà ọ là?
Nítorí èyí nínú ìbínú mi ni mo fún un yín ní ọba,
Ẹ̀bi Efraimu ni a tí ko jọ
Ìrora bí obìnrin tó fẹ́ bímọ ti dé bá a,
“Èmi yóò rà wọ́n padà kúrò lọ́wọ́ agbára isà òkú.
Bí ó tilẹ̀ gbilẹ̀ láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀
Ará Samaria gbọdọ̀ ru ẹ̀bi wọn,