Ní ọjọ́ ìkẹyìn
Copywork input for chapter 4 verse 1
Your input is saved to this browser automatically.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò wá,
Copywork input for chapter 4 verse 2
Your input is saved to this browser automatically.
Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn,
Copywork input for chapter 4 verse 3
Your input is saved to this browser automatically.
Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yóò jókòó lábẹ́ àjàrà rẹ̀
Copywork input for chapter 4 verse 4
Your input is saved to this browser automatically.
Gbogbo àwọn ènìyàn ń rìn,
Copywork input for chapter 4 verse 5
Your input is saved to this browser automatically.
“Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí,
Copywork input for chapter 4 verse 6
Your input is saved to this browser automatically.
Èmi yóò dá àwọn arọ sí fún èyí tókù,
Copywork input for chapter 4 verse 7
Your input is saved to this browser automatically.
Ní ti ìwọ, ilé ìṣọ́ agbo àgùntàn,
Copywork input for chapter 4 verse 8
Your input is saved to this browser automatically.
Kí ni ìwọ ha ń kígbe sókè sí nísinsin yìí?
Copywork input for chapter 4 verse 9
Your input is saved to this browser automatically.
Máa yí síyìn-ín sọ́hùn-ún nínú ìrora,
Copywork input for chapter 4 verse 10
Your input is saved to this browser automatically.
Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ọ̀pọ̀lọpọ̀ Orílẹ̀-èdè kó ara wọn jọ sí ọ.
Copywork input for chapter 4 verse 11
Your input is saved to this browser automatically.
Ṣùgbọ́n wọn kò mọ
Copywork input for chapter 4 verse 12
Your input is saved to this browser automatically.
“Dìde, kí ó sì máa pa ọkà ìwọ ọmọbìnrin Sioni,
Copywork input for chapter 4 verse 13
Your input is saved to this browser automatically.