Ọlọ́gbọ́n ọmọ gba ẹ̀kọ́ baba rẹ̀,
Copywork input for chapter 13 verse 1
Your input is saved to this browser automatically.
Láti inú èso ẹnu rẹ̀ ènìyàn ń gbádùn ohun rere,
Copywork input for chapter 13 verse 2
Your input is saved to this browser automatically.
Ẹnikẹ́ni tí ó ṣọ́ ẹnu rẹ̀ pa ẹnu ara rẹ̀ mọ́,
Copywork input for chapter 13 verse 3
Your input is saved to this browser automatically.
Ọkàn ọ̀lẹ ń fẹ́, ṣùgbọ́n kò rí nǹkan kan,
Copywork input for chapter 13 verse 4
Your input is saved to this browser automatically.
Olódodo kórìíra ohun tí í ṣe irọ́,
Copywork input for chapter 13 verse 5
Your input is saved to this browser automatically.
Òdodo ń ṣamọ̀nà ènìyàn olóòtítọ́ inú,
Copywork input for chapter 13 verse 6
Your input is saved to this browser automatically.
Ènìyàn kan díbọ́n bí ẹni tí ó ní ọrọ̀ síbẹ̀ kò ní nǹkan kan
Copywork input for chapter 13 verse 7
Your input is saved to this browser automatically.
Ọrọ̀ ènìyàn le è ra ẹ̀mí rẹ̀
Copywork input for chapter 13 verse 8
Your input is saved to this browser automatically.
Ìmọ́lẹ̀ olódodo tàn roro,
Copywork input for chapter 13 verse 9
Your input is saved to this browser automatically.
Ìgbéraga máa ń dá ìjà sílẹ̀ ni
Copywork input for chapter 13 verse 10
Your input is saved to this browser automatically.
Owó tí a fi ọ̀nà èrú kójọ yóò ṣí lọ,
Copywork input for chapter 13 verse 11
Your input is saved to this browser automatically.
Ìrètí tí ń falẹ̀ máa ń mú kí ọkàn ṣàárẹ̀
Copywork input for chapter 13 verse 12
Your input is saved to this browser automatically.
Ẹni tí ó kẹ́gàn ẹ̀kọ́ yóò jìyà rẹ̀
Copywork input for chapter 13 verse 13
Your input is saved to this browser automatically.
Ìkọ́ni ọlọ́gbọ́n jẹ́ orísun ìyè,
Copywork input for chapter 13 verse 14
Your input is saved to this browser automatically.
Òye pípé ń mú ni rí ojúrere,
Copywork input for chapter 13 verse 15
Your input is saved to this browser automatically.
Gbogbo olóye ènìyàn máa ń hùwà pẹ̀lú ìmọ̀,
Copywork input for chapter 13 verse 16
Your input is saved to this browser automatically.
Ìránṣẹ́ búburú bọ́ sínú ìdààmú
Copywork input for chapter 13 verse 17
Your input is saved to this browser automatically.
Ẹni tí ó kọ ìbáwí yóò di tálákà yóò sì rí ìtìjú,
Copywork input for chapter 13 verse 18
Your input is saved to this browser automatically.
Ìfẹ́ tí a mú ṣẹ dùn mọ́ ọkàn
Copywork input for chapter 13 verse 19
Your input is saved to this browser automatically.
Ẹni tí ó ń bá ọlọ́gbọ́n rìn yóò gbọ́n
Copywork input for chapter 13 verse 20
Your input is saved to this browser automatically.
Òsì a máa ta ẹlẹ́ṣẹ̀,
Copywork input for chapter 13 verse 21
Your input is saved to this browser automatically.
Ènìyàn rere a máa fi ogún sílẹ̀ fún àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀,
Copywork input for chapter 13 verse 22
Your input is saved to this browser automatically.
Ilẹ̀ ẹ tálákà le è mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìre oko wá
Copywork input for chapter 13 verse 23
Your input is saved to this browser automatically.
Ẹni tí ó fa ọwọ́ ìbáwí sẹ́yìn kórìíra ọmọ rẹ̀
Copywork input for chapter 13 verse 24
Your input is saved to this browser automatically.
Olódodo jẹ́wọ́ títí ó fi tẹ́ ọkàn rẹ̀ lọ́rùn
Copywork input for chapter 13 verse 25
Your input is saved to this browser automatically.