Nígbà tí ìwọ bá jókòó láti bá ìjòyè jẹun,
Copywork input for chapter 23 verse 1
Your input is saved to this browser automatically.
Ìwọ a sì fi ọ̀bẹ lé ara rẹ ní ọ̀fun,
Copywork input for chapter 23 verse 2
Your input is saved to this browser automatically.
Má ṣe fẹ́ oúnjẹ dídùn rẹ̀:
Copywork input for chapter 23 verse 3
Your input is saved to this browser automatically.
Má ṣe ṣe làálàá láti lọ́rọ̀:
Copywork input for chapter 23 verse 4
Your input is saved to this browser automatically.
Ìwọ ó ha fi ojú rẹ lépa ohun tí kò sí?
Copywork input for chapter 23 verse 5
Your input is saved to this browser automatically.
Má ṣe jẹ oúnjẹ ẹni tí ó háwọ́,
Copywork input for chapter 23 verse 6
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí pé bí ẹni tí ń ṣírò ní ọkàn rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ó rí:
Copywork input for chapter 23 verse 7
Your input is saved to this browser automatically.
Òkèlè tí ìwọ jẹ ni ìwọ ó pọ̀ jáde,
Copywork input for chapter 23 verse 8
Your input is saved to this browser automatically.
Má ṣe sọ̀rọ̀ ní etí aṣiwèrè;
Copywork input for chapter 23 verse 9
Your input is saved to this browser automatically.
Má ṣe ṣí ààlà àtijọ́ kúrò;
Copywork input for chapter 23 verse 10
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí pé Olùràpadà wọn lágbára;
Copywork input for chapter 23 verse 11
Your input is saved to this browser automatically.
Fi àyà sí ẹ̀kọ́,
Copywork input for chapter 23 verse 12
Your input is saved to this browser automatically.
Má ṣe fa ọwọ́ ìbáwí sẹ́yìn kúrò lára ọmọdé,
Copywork input for chapter 23 verse 13
Your input is saved to this browser automatically.
Bí ìwọ fi pàṣán nà án,
Copywork input for chapter 23 verse 14
Your input is saved to this browser automatically.
Ọmọ mi, bí ọkàn rẹ bá gbọ́n,
Copywork input for chapter 23 verse 15
Your input is saved to this browser automatically.
Inú mi yóò sì dùn nígbà tí ètè rẹ̀ bá ń sọ̀rọ̀ títọ́.
Copywork input for chapter 23 verse 16
Your input is saved to this browser automatically.
Má ṣe jẹ́ kí àyà rẹ ó ṣe ìlara sí àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,
Copywork input for chapter 23 verse 17
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí pé ìgbẹ̀yìn ń bẹ nítòótọ́;
Copywork input for chapter 23 verse 18
Your input is saved to this browser automatically.
Gbọ́, ìwọ ọmọ mi, kí o sì gbọ́n,
Copywork input for chapter 23 verse 19
Your input is saved to this browser automatically.
Má ṣe wà nínú àwọn ọ̀mùtí;
Copywork input for chapter 23 verse 20
Your input is saved to this browser automatically.
nítorí pé ọ̀mùtí àti ọ̀jẹun ni yóò di tálákà;
Copywork input for chapter 23 verse 21
Your input is saved to this browser automatically.
Fetí sí ti baba rẹ tí ó bí ọ,
Copywork input for chapter 23 verse 22
Your input is saved to this browser automatically.
Ra òtítọ́, kí o má sì ṣe tà á;
Copywork input for chapter 23 verse 23
Your input is saved to this browser automatically.
Baba olódodo ni yóò yọ̀ gidigidi:
Copywork input for chapter 23 verse 24
Your input is saved to this browser automatically.
Jẹ́ kí baba rẹ àti ìyá rẹ ó yọ̀,
Copywork input for chapter 23 verse 25
Your input is saved to this browser automatically.
Ọmọ mi, fi àyà rẹ fún mi,
Copywork input for chapter 23 verse 26
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí pé panṣágà obìnrin ọ̀gbun jíjìn ni;
Copywork input for chapter 23 verse 27
Your input is saved to this browser automatically.
Òun á sì ba ní bùba bí olè,
Copywork input for chapter 23 verse 28
Your input is saved to this browser automatically.
Ta ni ó ni òsì? Ta ni ó ni ìbànújẹ́?
Copywork input for chapter 23 verse 29
Your input is saved to this browser automatically.
Àwọn tí ó dúró pẹ́ níbi ọtí wáìnì;
Copywork input for chapter 23 verse 30
Your input is saved to this browser automatically.
Ìwọ má ṣe wò ọtí wáìnì nígbà tí ó pọ́n,
Copywork input for chapter 23 verse 31
Your input is saved to this browser automatically.
Níkẹyìn òun á bu ni ṣán bí ejò,
Copywork input for chapter 23 verse 32
Your input is saved to this browser automatically.
Ojú rẹ yóò wò àwọn àjèjì obìnrin,
Copywork input for chapter 23 verse 33
Your input is saved to this browser automatically.
Nítòótọ́, ìwọ ó dàbí ẹni tí ó dùbúlẹ̀ ní àárín Òkun,
Copywork input for chapter 23 verse 34
Your input is saved to this browser automatically.
Ìwọ ó sì wí pé, “Wọ́n lù mí; kò dùn mí;
Copywork input for chapter 23 verse 35
Your input is saved to this browser automatically.