Ọmọ mi, pa ọ̀rọ̀ mi mọ́,
Copywork input for chapter 7 verse 1
Your input is saved to this browser automatically.
Pa òfin mi mọ́, ìwọ yóò sì yè
Copywork input for chapter 7 verse 2
Your input is saved to this browser automatically.
Kọ wọ́n sí ọwọ́ òsì rẹ, má ṣe fi jẹun
Copywork input for chapter 7 verse 3
Your input is saved to this browser automatically.
Wí fún ọgbọ́n pé, “Ìwọ ni arábìnrin mi,”
Copywork input for chapter 7 verse 4
Your input is saved to this browser automatically.
Wọn yóò pa ó mọ́ kúrò lọ́wọ́ obìnrin alágbèrè,
Copywork input for chapter 7 verse 5
Your input is saved to this browser automatically.
Ní ojú fèrèsé ilé è mi
Copywork input for chapter 7 verse 6
Your input is saved to this browser automatically.
Mo rí i láàrín àwọn aláìmọ̀kan
Copywork input for chapter 7 verse 7
Your input is saved to this browser automatically.
Ó ń lọ ní pópónà ní tòsí i ilé alágbèrè obìnrin náà,
Copywork input for chapter 7 verse 8
Your input is saved to this browser automatically.
Ní ìrọ̀lẹ́ bí oòrùn ṣe ń wọ̀,
Copywork input for chapter 7 verse 9
Your input is saved to this browser automatically.
Bẹ́ẹ̀ ni obìnrin kan jáde wá láti pàdé rẹ̀,
Copywork input for chapter 7 verse 10
Your input is saved to this browser automatically.
(Ó jẹ́ aláriwo àti alágídí,
Copywork input for chapter 7 verse 11
Your input is saved to this browser automatically.
bí ó ti ń já níhìn-ín ní ó ń já lọ́hùn ún
Copywork input for chapter 7 verse 12
Your input is saved to this browser automatically.
Ó dìímú, ó sì fẹnukò ó ní ẹnu
Copywork input for chapter 7 verse 13
Your input is saved to this browser automatically.
“Mo ní ọrẹ àlàáfíà ní ilé;
Copywork input for chapter 7 verse 14
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí náà ni n o ṣe jáde wá pàdé è rẹ;
Copywork input for chapter 7 verse 15
Your input is saved to this browser automatically.
Mo ti tẹ́ ibùsùn mi
Copywork input for chapter 7 verse 16
Your input is saved to this browser automatically.
Mo ti fi nǹkan olóòórùn dídùn sí ibùsùn mi
Copywork input for chapter 7 verse 17
Your input is saved to this browser automatically.
Wá, jẹ́ kí a lo ìfẹ́ papọ̀ ní kíkún títí di àárọ̀;
Copywork input for chapter 7 verse 18
Your input is saved to this browser automatically.
Ọkọ ọ̀ mi ò sí nílé;
Copywork input for chapter 7 verse 19
Your input is saved to this browser automatically.
Ó mú owó púpọ̀ lọ́wọ́
Copywork input for chapter 7 verse 20
Your input is saved to this browser automatically.
Pẹ̀lú ọ̀rọ̀ dídùn ó sì í lọ́nà;
Copywork input for chapter 7 verse 21
Your input is saved to this browser automatically.
Òun sì tọ̀ ọ́ lọ lẹsẹ̀ kan náà,
Copywork input for chapter 7 verse 22
Your input is saved to this browser automatically.
Títí tí ọ̀kọ̀ fi gún un ní ẹ̀dọ̀,
Copywork input for chapter 7 verse 23
Your input is saved to this browser automatically.
Nítorí náà báyìí ẹ̀yin ọmọ mi, tẹ́tí sí mi
Copywork input for chapter 7 verse 24
Your input is saved to this browser automatically.
Má ṣe jẹ́ kí ọkàn rẹ kí ó yà sí ọ̀nà rẹ̀,
Copywork input for chapter 7 verse 25
Your input is saved to this browser automatically.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn tí ó ti fà lulẹ̀.
Copywork input for chapter 7 verse 26
Your input is saved to this browser automatically.
Ilé e rẹ̀ ni ọ̀nà tààrà sí isà òkú,
Copywork input for chapter 7 verse 27
Your input is saved to this browser automatically.